FIBAN LAGOS

FIBAN LAGOS

Share

14/12/2021

Kílódé Tí Ilé-Ẹjọ́ Wọ́gilé Ìgbéyàwó Ìkòyí?
Ẹ̀yìn Ìyàwó Ò Mà Gbọdọ̀ Mẹníì🙄

👉 |fẹ́ràn👍| kọ-ọ̀rọ̀✍️| pín-in⚡

13/12/2021

Ìròyìn Àwòko Fiban Èkó News

(1) Ààrẹ Buhari, Jonathan péjú ní ìpàdé Ecowas.

(2) Ayu sọ pé Ẹgbẹ́ PDP yóò jáwé olúborí ní Ìpínlẹ̀ márùndínlọ́gbọ̀n ní ọdún 2023.

(3) Ṣọ̀ún Ògbómọ̀ṣọ́ wàjà.

(4) Obásanjọ́ ṣe ìdárò Ṣọ̀ún

(5) Ajọ Serap rọ lawan àti Gbàjàbíàmílà kí wọ́n wádìí bílíọ̀nù mẹ́wàá owó ìgbìmọ̀ aṣòfin.

(6) FRSC ṣe kìlọ̀kìlọ̀ fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ NURTW kí wọ́n bẹ̀rù òfin ìrìnà.

(7) Àwọn jàǹdùkú ń béèrè mílíọ̀nú kan owó orí ní Ìpínlẹ̀ Zamfara.

(8) Ilé iṣẹ́ ológun sọ pé àwọn jàǹdùkú kò jí àwọn ènìyàn gbé ní ojúnà Maiduguri sí Damaturu.

(9) Wọn ti rí Janet ọmọbìnrin tí wọn jí gbé ní ìlú Èkó.

(10) Wọ́n jí ẹ̀gbọ́n Sheikh Gumi gbé

(11) Ikú akẹ́kọ̀ọ́ ilé ìwé Dowen: ilé iṣẹ́ Ọlọ́pàá mú akẹ́kọ̀ọ́ márùn-ún àti òbí mẹ́ta.

(12) Wọ́n ká ìdí àádọ́rin òògùn olóró kookéènì mọ arìnrìn-àjò Italy lọ́wọ́.

(13) Orílẹ̀ èdè UAE bẹ ìjọba Nàìjíríà kí wọ́n fi ààyè gba Emirate ni Nàìjíríà.

(14) Orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fi òfin de Canada, Saudi Arabia àti àwọn orílẹ̀ èdè ìmíràn.

(15) Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Totheham, Man United nífẹ̀ẹ́ sí adẹ̀hìnmú Chelsea Christensen.

(16) NFF júwe ilé fún Rohr, wọ́n gba Eguavon gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá fìdíhẹ́.

À rí Ajé Jẹun lónìí (Àṣẹ)

Àyìnlá Omi

Want your business to be the top-listed Media Company in Lagos?
Click here to claim your Sponsored Listing.

Telephone

Address


Lagos